BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Mi ò kí ń ṣe aláìmoore bíi Aregbesola, mo máa ṣàtìlẹ́yìn fún Tinubu fún sáà kejì – Igboho
Igboho lo sọ ọrọ yii lasiko to ṣabẹwo si ọọfisi awọn ọdọ ẹgbẹ oṣelu APC lorilẹede Ghana.
'Èèwọ̀ ni, n kò gbọdọ̀ f'ojú kan ìyá mi láàyè tàbí ní okú'
Yatọ si eyi, eewọ tun ni fun ọba naa lati ri ọmọ tuntun ti iyawo rẹ ba bi, titi ọmọ naa yoo fi pe oṣu mẹfa.
Wo ohun tí òfin nọ́mbà ìdánimọ̀ tí Aarẹ ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù túmọ̀ sí fún ọ
Tinubu lasiko to n buwọlu aba naa lọjọ Ẹti ni ilu Abuja sọ pe ofin tuntun naa yoo mu aabo to peye ba orilẹ ede tuntun ti wọn n gbero fun Naijiria, ti yoo si tun mu eto ọrọ aje Naijiria.
A máa tó gba ọkọ̀ òfurufú láti dá ààbò bo ìpínlẹ̀ Oyo, a tún máa ṣí àwọn ilé ẹ̀kọ́ padà láìpẹ́ - Makinde
Makinde sọ eyi ninu atẹjade rẹ fun ti oṣu Kẹfa, ọdun 2026 nibi to ti sọrọ nipa eto aabo ni ipinlẹ Oyo atawọn igbesẹ ti wọn n gbe lati gba itusilẹ awọn akẹkọọ ati olukọ tawọn ajinigbe ji gbe ni ilu Esinele ati Yawota ni ijọba ibilẹ Oriire.
Ìjọba Oyo fòpin sí òfin kónílé-ó-gbélé tó gbé kalẹ̀ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́wàá
Ṣaaju ni atẹjade kan ti milẹ titi loju opo Facebook pe pasitọ kan lo n ko ohun ija oloro fun awọn agbesunmọmi naa bo tilẹ jẹ pe atẹjade naa ko kede orukọ pasitọ ọhun tabi ibi to n gbe.
Ìjọba ti bẹ̀rẹ̀ sí í wó àwọn ilé tó ti rẹ̀ nítòsí èyí tó wo pa èèyàn mẹ́sàn-án l'Eko
Ọjọ Ẹti ni igbesẹ awọn ile ti wọn n wo naa ti wọn ni ewu loko Longẹ ni wọn, bẹrẹ.
Mọ̀ sí i nípa Ibikunle, Akọni Ìlú Ibadan tó jẹ́ Balogun kan ṣoṣo tó rẹ́yìn Ààrẹ Ọ̀nà Kakaǹfò
Ibikunle ja ogun Ijaye, o si tun ja ogun Fulani niluu Osogbo, bakan naa ni o tun ja ogun Ijebu Ẹrẹ, ogun Ara, ogun Kutujẹ eyi ti i ṣe ogun ti Ibikunle ja gbẹyin ki ọlọjọ to de.
A ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì iléeṣẹ́ OGTV láti kọ́ ọ lẹ́kọ̀ọ́ ni - Afurasí
CP Bode Ojajuni ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ogun, sọ fawọn akoroyin l'Ọjọbọ pe awon afurasi naa jẹwọ pe awon pa Kitan lati kọ ọ lẹkọọ ni
Ìtàn Mánigbàgbé: Ohun mẹ́rìnlá nípa ọdún Bẹbẹ to máa ń wáyé fún ọdún mẹ́ta lẹ́yìn tí Aláàfin kan bá lo àádọ́ta ọdún lórí ìtẹ́
BBC News Yorùbá ṣe àgbéyẹ̀wò ìtàn mánigbàgbé nípa ọdún Bẹbẹ tó máa ń wáyé nílùú Oyo láyé ijọ́un àti kókó ohun mẹ́rìnlá nípa ọdún náà.
Àwọn agbébọn ló dojú ààbò ilẹ̀ Yorùbá délẹ̀, digbí là wá lẹ́yìn Sunday Igboho - Afenifere
Atẹjade kan ti agbẹnusọ egbẹ Afenifere, Jare Ajayi fi sita lọjọbọ, ọjọ Kẹẹdọgbọn, oṣu Kẹfa, ọdun 2026 sọ pe Igboho ko dunkoko mọ iran kankan bikoṣe awọn eeyan ati ẹgbẹ ti wọn n da alaafia ilẹ Yoruba laamu.
Kí ló mú àwọn awakọ̀ tírélà dí ojú ọ̀nà márosẹ̀ Eko sí Ore lọ dé Benin pa? Àlàyé rèé
Ọpọ awakọ ero, awakọ adani atawọn ero ọkọ lo foju wina idaamu nla latari iṣẹlẹ naa fun ọpọlọpọ wakati.
Ìjọba Ondo gbẹ́sẹ̀lé èsì ìdánwò akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́tàdínlógún torí fídíò àṣemáṣe tó gba orí ayélujára
Lara awọn fidio naa ṣafihan bi awọn akẹkọọ ọkunrin ṣe bẹrẹ si ni da gbogbo igboro ru lẹyin ti wọn pari idanwo naa, ti wọn si lọ ba awọn akẹkọọ ni ile ẹkọ mii ja.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ṣé òótọ́ ni àwọn ọlọ́pàá ń kan sáárá sáwọn agbébọn lásìkò tí wọn ń kọjá lórí ọ̀pọ̀ ọ́kadà lójú pópó?
Ṣaaju ni fidio kan ti n lọ lori ayelujara eyi to ṣafihan bi awọn eeyan kan, ti wọn pọ biba lori ọkada, ṣe n kọja lẹgbẹ awọn ọlọpaa, ti awọn ọlọpaa naa si n kan saara si wọn bi wọn ṣe n kọja.
Ìgbésẹ̀ wo ló kàn lẹ́yìn tílé aṣòfin àgbà buwọ́lu ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀?
Olori ile aṣofin agba, Godswill Akpabio, lo kede bẹẹ lẹyin ti ida meji ninu mẹta awọn aṣofn buwọlu ofin idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ. lẹyin ibo ti wọn di lori rẹ ninu ile naa.
Ọ̀daràn ni ẹnikẹ́ni tó bá ń gbé nínú igbó, ohun tí a máa ṣe fún wọn rèé... - Sunday Igboho
Sunday Igboho parọwa yii nigba to ṣe abẹwo si aafin Okere ti ilu Saki lasiko to lọ beere fun atilẹyin awọn Ọba naa lati koju iwa ijinigbe to ti di tọrọ fọnka sile ni awọn igbo o yi ilẹ Yoruba ka.
Báwọn ọmọ Nàíjíríà ṣe wà nínú ìbẹ̀rù àti ìpayà ní South Africa, ìṣí kejì wọn padà délé láàrin gbèkéde ìparí oṣù tí wọn fún wọn
Wilson sọ fun BBC pe awọn ẹgbẹ ọmọ ilẹ South Africa ni awọn maa lọ lati ojule sojule lati ṣe ayẹwo iwe igbeluu awọn ajoji.
Wọ́n yìnbọn pa ọkọ mini torí wọ́n ní kó wá rí olóṣèlú APC kan àmọ́ tó yarí kanlẹ̀ - Ìyàwó olóògbé
Atẹjade kan ti gomina Adeleke fi soju opo X rẹ sọ pe Aderogba to jẹ iyawo Aderogba Ajayi sọ pe oun wa pẹlu ọkọ oun ni alẹ ọjọ ti iṣẹlẹ naa waye.
Teslim Ajimobi, àbúrò Abiola Ajimobi jáde láyé lọ́jọ́ tó pé ọdún mẹ́fà tí ẹ̀gbọ́n rẹ̀ kú
Ilu London nilẹ United Kingdom ni oloogbe Teslim Ajimobi ti jade laye lai ti pe aadọrin ọdun.
Ọ̀nà wo ni ìṣéde tíjọba Oyo ṣe yóò gbà nípa lórí aráàlú láwọn ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́wàá tọ́rọ̀ kàn?
BBC Yoruba kan si awọn eeyan ti wọn n gbe ni Igboho atawọn ijọba ibilẹ ti ọrọ naa kan lati mọ ipa ti isede ijọba yoo ni lori ọrọ aje ati igbayegbadun wọn.
"Wọ́n yìnbọn pa ọmọ wa ní ṣọ́ọ̀bù ìyá rẹ̀ torí ẹnìkan dé fìlà yẹ́lò tó jẹ́ tẹgbẹ́ Accord l'Osun, mo fẹ́ ìdájọ́ òdodo"
BBC News Yoruba fi gba ilu Ilobu lọ lati tan imọlẹ si isẹlẹ yii, ka le mọ awọn eeyan to wa nidi isẹlẹ naa.
Kí ló dé tí UK ń pààrọ̀ Olóòtú ìjọba léraléra?
Ki lo fa ayipada yii? O ni idi kan pataki ti ayipada yii fi n waye fun awọn Olootu ijọba mẹfa ti wọn fi ipo wọn silẹ laaarin ọdun mẹwaa yii.
Oru àmújù ṣekúpa èèyàn ogójì nilẹ̀ France
Ni France, ajọ Météo France sọ pe ọjọ Aje ni oru naa mu julọ, wọn si ti fi ikilọ sita fun idaji orilẹede naa bayii.
Fídíò, "Búrẹ́dì ni ọkọ mi lọ rà fún àkọ́bí wa, tí wọ́n fi ṣá a pa ní ọ̀sẹ̀ kan lẹ́yìn ìkómọ ọmọ wa kejì", Duration 9,37
Opo meji, Abosede Olawoye ati Ojo Bunmi Abolanle, sọ iriri apanilẹkun ti wọn koju lẹyin ti ọkọ wọn ti jade laye lati sami ayajọ awọn opo to ko lonii.
Ọkùnrin kan rèé tó ti wà lórí ìdúró fún ọdún márùn-ún láì jòkòó tàbí dùbúlẹ̀
Daulat Giri Ji Maharaj jẹ ọkan lara ọmọ ẹgbẹ Khareshwari, ẹgbẹ ti awọn eeyan maa n jẹjẹẹ lati wa lori iduro fun igba tabi akoko kan lojuna ati fọ ọkan wọn mọ lati ni ibaṣepọ ẹmi pẹlu Oriṣa Shiva.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Àlàyé lórí báwọn ọ̀dọ́ kan ṣe fi ipá mú abílékọ jáde ní àhámọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì dáná sun ún
Iroyin sọ pe nibi ipejọpọ kan ti wọn ti n waasu ni obinrin ọhun wa tawọn ọdọ kan fi fẹsun kan an wi pe o fẹ ji ọmọ gbe.
Kí ló fa ìbúgbàmù tó wáyé ní Eko tó dá ìbẹ̀rù àti ìdààmú sílẹ̀?
Awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ salaye pe ọkunrin kan to ni ọkọ Toyota Sienna to paaki sita mọjumọ lo fẹ gbe ọkọ rẹ jade ki ado oloro naa to bu gbamu labẹ ọkọ rẹ lẹyin to ṣina si ọkọ naa.
Ẹgbẹ́ Arewa fọnmú lórí ìdúnkookò Sunday Igboho fáwọn Fulani pé yóò lẹ́yìn, Igboho fèsì padà
Ẹgbẹ Arewa atawọn ẹgbẹ Fulani mii fẹsun kan Igboho pe se lo n fi ẹsun iwa ọdaran tawọn kan n n hu, kan gbogbo odidi iran Fulani eyi to le dakun aabo to mẹhẹ.
Ta ni yóò di Olóòtú ìjọba tuntun ní UK, báwo ni wọn yóò ṣe yàn-án?
Andy Burnham, ẹni tii se Mayor tẹlẹ nilu Greater Manchester lo tete kede pe oun fẹ dije sipo olootu ijọba naa.
Amẹrika fòpin sí ìrànwọ́ rẹ̀ láti gbógun ti àrùn HIV/AIDS ní South Africa
O le ni miliọnu mẹjọ awọn ọmọ ilẹ South Africa to n gbe pẹlu arun HIV, eyi to jẹ orilẹede ti aarun naa pọ si julọ ni gbogbo agbaye.
Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?
Titọ atọ fun ọkunrun lasiko to n ba sun lọwọ ko ki n ṣe nnkan to buru, gẹgẹ bii awọn onimọ ilera ṣe ṣalaye.
A ò gba èsì ìbò tó gbé Oyebanji wọlé fún sáà kejì, ètò ìdìbò náà kún fún èrú - AAC
Atẹjade ti alaga ẹgbẹ oṣelu AAC tẹka ipinle Ekiti, Makinde Folorunso fi lede lọjọ Abamẹta, Ogunjọ, oṣu Kẹfa lẹyin ti eto idibo naa pari fẹsun kan pe awọn iwa ko tọ to waye nibi eto idbo naa ko kere.
Father's Day: Kí ni pàtàkì àyájọ́ ọjọ́ bàbá àti ìtàn tó rọ̀ mọ?
Ọjọ Aiku kẹta ninu oṣu Kẹfa ni wọn maa n ṣa ayajọ naa ni ọpọ orilẹede.
Wo kókó ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Abiodun Oyebanji, olùdíje gómìnà fẹ́gbẹ́ APC tó wọlé sáà kejì l'Ekiti
Apapọ ibo to ni jẹ 319, 224, òun sì lo ní ibo to pọ julọ ni gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ merindinlogun to wa ni ìpínlẹ̀ Ekiti.











































































