BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
Èmi ò sọ̀rọ̀ tàbùkù Olubadan o, ọmọ ni mo jẹ́ sí Ọba Rashidi Ladọja - Bayọ Adelabu sọ̀rọ̀ síta lẹ́yìn tí wọ́n ní ó sọ̀kò ọ̀rọ̀ ránṣẹ́ s'Olubadan nítorí òṣèlú
4 Èbibi 2026
Ààrẹ Tinubu ló ni àsìkò ti tó fún mi láti lọ dupò gómínà Oyo- Adelabu
3 Èbibi 2026
Ẹbí ọlọ́kadà tó kú n'Ibadan lẹ́yìn táwọn ọlọ́pàá dá a dúró ké gbàjarè, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé nǹkan tó ṣẹlẹ̀
2 Èbibi 2026
1:02
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 1,02
wákàtí 4 sẹ́yìn
4:29
Fídíò,
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
, Duration 4,29
24 Ìgbé 2026
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
24 Ìgbé 2026
Erin kọlu ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Oyo, pa èèyàn kan, ẹlòmíì di àwátì
24 Ìgbé 2026
Gbọin-gbọin ni a wà lẹ́yìn Makinde bí òkè, àhesọ ọ̀rọ̀ lásán n'ìròyìn tó ní a fẹ́ yọ ọ́ nípò – Ilé Aṣòfin Oyo
23 Ìgbé 2026
Mínísítà fọ́rọ̀ ohun àmúsagbára Adebayo Adelabu ṣàlàyé ìdí tó fi kọ̀wé fipò sílẹ̀
23 Ìgbé 2026
A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan
20 Ìgbé 2026
Ọba kì í ṣe òṣèlú, Olubadan, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ kẹ́ ẹ má baà mú àrífín wá - Balogun Olubadan
18 Ìgbé 2026
"Ẹ̀yin ọ̀dọ́ tí ẹ̀ ń kún pé bí Toun Soetan ṣe ń kọrin ń di yín lọ́wọ́ láti dárà nínú ìjọ, ó ti lọ, ẹ wá dárà yín ká rí i"
17 Ìgbé 2026
Ibà ọ̀rẹ̀rẹ̀ (Lassa Fever) wọ ìpínlẹ̀ Oyo, wo ọ̀nà márùn-ún láti dènà rẹ̀
16 Ìgbé 2026
Dárúkọ pẹ̀lú ẹ̀rí tó dájú àwọn tó fi rìbá lọ̀ ọ́ láti gbé ìgbésẹ̀ ìyọnípọ̀ Makinde bíbẹ́ẹ̀kọ́... - Olórí ilé aṣòfin àná
15 Ìgbé 2026
Àwọn ìdí rèé tí gómìnà kan fi le yọ ọba nípò lábẹ́ òfin
13 Ìgbé 2026
3:55
Fídíò,
Arọ́bafin ni Sẹ́nétọ̀ Adeseun ni mo fi ní kó gáfárà fún ipò Mayegun ìlú Ogbomoso – Soun Ghandi Laoye
, Duration 3,55
10 Ìgbé 2026
4:00
Fídíò,
Soun Ogbomoso ti pín ìlú yẹ́lẹyẹ̀lẹ pẹ̀lú ìwà kíìgbọ́-kìígbà rẹ̀, èmi ò sì lè báa ṣiṣẹ́ mọ́ ni mo ṣe kọ̀wé fipò Máyégún sílẹ̀ -Sẹ́nétọ̀ Adeseun
, Duration 4,00
10 Ìgbé 2026
Mi ò bá Makinde àti Olubadan jà, ìdí rèé táwọn èèyàn kò fi rí mi pọ̀ mọ́ Gómìnà àti Ọba Ladoja - Alaafin
8 Ìgbé 2026
Àwọn afurasí darandaran ṣá àgbẹ̀ sínú oko rẹ̀ l'Ogbomoso lẹ́yìn tó ní wọn kò gbọdọ̀ da ẹran níbẹ̀
8 Ìgbé 2026
Makinde gbé Adé àti Ọ̀pá Àṣẹ fún Ọba mẹ́ta tó wà lójú òpó Olubadan, bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn Ọba náà ò yọjú
4 Ìgbé 2026
Tánkà agbépo tó sọ ìjánu rẹ̀ nù kọlu kẹ̀kẹ́ Maruwa lọja Oje n'Ibadan, èèyàn mẹ́ta kú, àwọn mìíràn kán léegun ẹ̀yìn
24 Ẹrẹ̀nà 2026
Makinde kéde ₦10,000 owó ìrànwọ́ fáwọn òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Oyo torí ọ̀wọ́ngógó epo bẹntiróòlù
23 Ẹrẹ̀nà 2026
Ṣé lóòótọ́ ni pé èpè Alaafin Aole sì ń ja Yorùbá títí di òní?
21 Ẹrẹ̀nà 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
More:
News
•
Sport
•
Weather
•
Worklife
•
Travel
•
Future
•
Culture
•
World
•
Business
•
Technology
•
Science_and_environment
•
Entertainment_and_arts
×